Ìlú ti Bahia jẹ́ ìlú ti èyìàn dúdú pọ̀ jùlọ ni agbaye lẹ́hìn Afirika
Orúkọ tèmi ni Olúkọ agba Adelson de Brito ti gbogbo yin mọ̀ si Mawo Adelson
Emi ni Olùkọ́ Èdè àti Àṣà Yorùbá-Nàgó.
Mo si tún jẹ́ olori Ẹ̀sin Ibilẹ̀ Òrìṣà ati
Vodun ní ìlú Salvador, ti olú-ìlú ipinlẹ̀ Bahia.
O ti pe ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ọdún bayii ti owo ẹrú ti bẹrẹ jakejado agbaye,
tawọn orilẹede
agbaye si ti se ọpọ eto lati se ayẹyẹ náà.
Fún
àpẹẹrẹ, ni oşù keji ọdún ní orílẹ̀-èdè Amẹ́rika (USA)
jẹ́ àsìkò ti wọn máa şe ìrántí ìtàn àwọn adúláwọ̀ ti o jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè
Amẹ́rika.
Brasili tíi
ṣé orílẹ̀-èdè kéji ti àwọn
aláwọ̀ dúdú pọ̀ sí jùlọ àgbáyé lẹ́hìn orilẹ̀-èdè Naijiria.
Ni ode oni
ni ìlú Brasili, ani bi ọgọ́ta
millionu àwon ènìyàn dúdú tojẹ́ ọmọ ọmọ àwọn ẹrú tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n, kosi ohun kankan ti ijọba maa şe fún ìrántí ìtàn àwọn adúláwọ̀ ti o jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè yìí.
Salvador
lokọ́kọ́ jẹ́ Olú ìlú
Brasili lati Ọdún 1549 titi
di Ọdún 1763, elekeji ni Ìlú Rio de
Janeiro, lati Ọdún 1763 titi di 1960, lẹ́hìn igbana, Brasilia titi di asiko yìí.
Ìlú Salvador jẹ́ dida silẹ̀ ni Ọjọ́ 29, Oṣù Kẹta, Ọdún 1549, gẹgẹbi Òlu ìlú Brasili ni Aiye àwọn oyinbo amunisin Pọrtugi.
Wọn
mú Ìlú yìí gẹgẹbi Olú Ìlú nitori osúnmọ́ eti òkun ti anpe ni Bahia de Todos os Santos.
Ṣe
o mọ̀ wípè
ni aye atijọ́,
làkókò oko ẹrú ni ìlú yìí, àwọn ọmọ káàrò-oòjíire lò èdè kanna fún ibaraẹninsọ̀rọ̀ laarin ara wọn?
Ṣe
o mọ̀ wípè pè nitori
wọn a n
pé “Ànàgó” abi Nàgó, èdè ti wọn
lò tún a pè “èdè Ànàgó” abi “Nàgó”?
Ó se pàtàkì láti mọ díẹ̀ nípa
ìtàn àwọn ènìyàn Ànàgó ni Ìlú yìí.
Ìdí èyí ni pé yóò jẹ́ ohun ìrànlọ́wọ́ fún
ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan tó yẹ ní mímọ̀ nínú ìtàn aláwọ̀
dúdú ti wọn ń ngbe ni ìlú yìí.
Fún ìdí pàtàkì yìí, n ó ò pín akosilẹ̀ yìí si ọ̀nà mẹ́tà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀.
1. Àwọn
imale Nàgó àti ọ̀rọ̀ oṣelú ti ìlú Salvador làkókò oko ẹrú
2. Àwọn
oníṣòwò Nàgó;
3. Àwọn
ẹsin ibilẹ̀ Ànàgó: àwọn oloorìṣà
àti ẹsin ibilẹ̀ Vodun
Ni osẹ to n bọ̀ a maa kọ̀
yin nipa Àwọn imale Nàgó àti ọ̀rọ̀ oṣelú
làkókò oko ẹrú ni ìlú yìí
O dabọ!
Tradução
A Cidade da Bahia é a Cidade mais preta do mundo fora da África
Meu nome é Adelson de Brito,
mais conhecido como Mawo Adelson
Sou professor de Língua e
Cultura Ioruba-Nàgó.
Também sou Sacerdote da Igreja tradicional Orixá e Vodun em Salvador, capital do Estado da Bahia.
Já se passaram quase 500 anos
desde que o tráfico de escravos
começou em todo o mundo, e muitos países ao redor do mundo planejam eventos
para marcar a data.
Por exemplo, o mês de
fevereiro nos Estados Unidos da América (EUA) é uma época para comemorar a
história dos negros americanos.
O Brasil é o segundo país mais negro do mundo, depois da
Nigéria.
Hoje, no Brasil, cerca de 60
milhões de negros são descendentes de escravos, mas nem assim o governo faz qualquer evento para comemorar a história dos
negros.
Salvador foi a capital do
Brasil de 1549 a 1763, a segunda foi o Rio de Janeiro, de 1763 a 1960, e depois
Brasília, até hoje
Salvador foi fundada em 29 de março de 1549,
como capital do Brasil na colônia portuguesa.
A cidade foi considerada a capital pela
proximidade com a Bahia de Todos os Santos.
Você sabia que nos tempos
antigos, durante o tráfico de escravos nesta cidade, os filhos de Oduduwa usavam a mesma linguagem para
se comunicarem?
Você sabia que se eles eram chamados de "Anago" ou
"Nago", porque a língua que eles usam também se chamava "Anago" ou
"Nago"?
É importante conhecer um pouco
da história do povo Nagô nesta cidade.
Isso porque será útil conhecer a história dos negos que vivem nesta cidade.
Por esse motivo, vou dividir este tópico em
três partes.
1. Os muçulmanos Nagô e a política no tempo da escravidão
2. Os Comerciantes Nago;
3. As Religiões tradicionais Nagô: A Religião Orixá e o Culto aos Voduns Candomblé
Na próxima semana, estaremos falando sobre: Os muçulmanos Nagô e a política no tempo da escravidão.
Atá a próxima!

Comentários
Postar um comentário